STELLA HASSAN-EJIRELE IFE-OODAYE COMMUNICATIONS July 31, 2018STELLA HASSAN-EJIRELE. IFE- OODAYE COMMUNICATIONS. ÀṢÀ ÈDÈ ÌṢE ILẸ̀ WÁ LO JẸ WỌN LÓGÚN Yorùbá bọ wọ́n ní naninani nani , ohùn aní là nani...Read More
Christopher Oladogba Aare Egbeomouk ṣe ìgbéyàwó fún ọmọ July 29, 2018CHRISTOPHER OLADOGBA AARE ẸGBẸ́ỌMỌIFẸUK ṢE ÌGBÉYÀWÓ F'ỌMỌ AYÉ GBỌ Ọ̀RUN MỌ. Eto ìgbéyàwó láyé ọba Olúwa lo fi lè lẹ pẹlu àṣẹ ni. Pẹpẹ...Read More
DÍẸ̀ NÍNÚ ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ỌLỌ́WỌ́ APC BỌ AṢỌ ẸGBẸ́ OSELU WỌN SILẸ GBÉ AṢỌ ALABURODA PDP WỌ. July 24, 2018Ọwọ̀ kọ, kò f'ẹnu kò laarin awọn ọmọ ẹgbẹ́ Ọlọ́wọ̀ APC ní ilé ìgbìmò asofin àgbà àti kékeré ni Olú ìlú wá Abuja. Àkàrà Dórí Akayin Ó D&...Read More
DÍẸ̀ NÍNÚ ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ỌLỌ́WỌ́ APC POHÙN DÁ BỌ AṢỌ ÌPÌN ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC SILẸ NÍ ILE IGBIMO ASOJU SOFIN July 24, 2018 Ọwọ̀ kọ, kò f'ẹnu kò laarin awọn ọmọ ẹgbẹ́ Ọlọ́wọ̀ APC ní ilé ìgbìmò asofin àgbà àti kékeré ni Olú ìlú wá Abuja. ...Read More
ÈTÒ IKOWOJỌ FÚN ILÉ ÀWỌN ARÚGBÓ July 19, 2018 ÈTÒ IKOWOJỌ FÚN ILÉ ARÚGBÓ. òréré layé, ọ̀rọ̀ àwọn àgbà ní. Ìrírí ni mójú àgbà jin Karí ilé ayé gbé pẹ̀lú irọru...Read More
ILE ÌTURA ÒṢÙMÀRÈ SKYRAINBOW COURTYARD DID ṢÍṢÍ NÍ ÀNÁ ÒDE YÌÍ NÍ ÌLÚ ILÉ-IFÈ July 15, 2018 ILE ÌTURA ÌGBÀLÓDÉ ÒṢÙMÀRÈ SKYRAINBOW COURTYARDS DI ṢÍṢÍ LÀNÀ ODE YÌÍ NÍ ÌLÚ ILÉ-IFÈ. ilé ìwé ìròyìn Odidere Ayeko...Read More
DÓKÍTÀ FAYEMI DI AJẸLẸ TUNTUN NÍ ÌPÍNLÈ ÈKÌTÌ July 15, 2018 FAYEMI FA'KỌYỌ GB'OÚNJẸ F'ẸGBẸ Ó TÚN GBA'WO BỌ NÍNÚ ÈṢÌ IBO ÈKÌTÌ TI ÌJỌBA AJẸLẸ TI ÌPÍNLÈ EKITI. Ilé ìwé Ir...Read More
HRH JAMES OYÈBÁMIJÍ ADEYEFA JAARAN TI ILẸ̀ ÌFẸ́ JÁDE LÁYÉ July 10, 2018BÀBÁ JAARAN ADIMULA TI ILẸ̀ IFÈ PA HRH JAMES OYÈBÁMIJÍ ADEYEFA KÍ AYÉ PÉ OD'IGBA Ó ṢE ỌMỌ ỌGỌ́RÙN-ÚN ATI MEWA NÍ BÀBÁ Ń ṢE KÍ IKÚ TO Y...Read More
ÌYÁ AGBA OLUDASILE ÌWÉ IROYIN AWIKONKO KÍ AYÉ PÉ OD'IGBA Ó ṢE* *Yoruba bọ wọ́n ní ẹ kú ìrójú ń gbẹyín ẹ kú ewu ọmọ. Bẹẹ naa ni ìwé mimọ sọ* *Ìyá àgbà Awikonko lójú ọl'̀rọ̀ tí fi ilẹ bora bí aṣọ, ìyá Agba tí lọ rá ìwo ẹṣin wá. Wọ́n ti dé ibusọ tí wọ́n, wọ́n ti sọ kalẹ nínú ọkọ̀ ayé yìí. Ó rí bẹ nítorí wípé gbogbo ìwé mimọ fi idi rẹ múlẹ̀ pé dandan ni ikú jẹ fún àwa ẹ̀dá asemi, adìẹ irana sì ni pẹ̀lú kí ṣe ohun a jẹ gbé . A ń bẹ adẹda, Aṣẹ̀dá pé kò fi ọdún kún ọdún, ìgbà kún ìgbà fún àwa tó kù láyé, ká tẹ ilẹ̀ yí pé, ká dúró ṣe ohun rere lórí òkè eepe, ká tẹ pẹpẹ, ká f'ọwọ́ pawu, ká ferigi jobi, ká fi ọ̀pá ṣe ìkẹta ẹsẹ̀ lọ́jọ́ ogbó bí ti ìyá Agba Awikonko ká tó lọ láyé* . *Fún ìdí èyí èmi Oludasile àti olùdarí ilé isẹ ìwé ìròyìn Odidere Ayekooto ń fi àsìkò yí báyin kẹ́dùn fún lílọ tí ìyá àgbà lọ ibi àgbà ń ré . Ó dá mi lójú pé ọkàn nínú àwọn ọmọ ọmọ ọmọ ìyá àgbà ni Awikonko ń ṣe. Ọba Èdùmàrè yio dúró tì gbogbo ẹyin ẹbi ti òkú ọrùn fi silẹ lọ*. *Ní orúkọ Èmi àti àwọn ìdílé mi Alhaji Saliu Oyewole-Erinle àti ìyáàfin Ọtún iyalode Hon Faridat Taye Oyewole-Erinle báyin kẹ́dùn, àtún ń fi àdúrà dúró tì yín ṣinṣin ni àsìkò ìdárò ipapoda tí ìyá àgbà tí ẹ wà yi àti kárí gbogbo ẹbí yín lápapò pé ẹ kú idele ìyá onínú ire tí ó ré ìwàlàaṣà* *A wá ń fi àsìkò yí bẹ adẹda fún gbogbo àwa ti a n bá Awikonko daro tí ìyá wọn àgbà pé kí elédùmarè ó jẹ ki ọdún ó jìnnà sì ara wọn fún ẹnì kọ̀ọ̀kan wa*.àmín *Awikonko ọmọ l'oku, a baja ni ọrùn, Ọlọ́run a bò yín ní àṣírí*. *Ẹ má gbàgbé láti fi ìwé ìpè ransẹ sì gbogbo àwa olólùfẹ́ yin nígbà tí ẹ bá ń ṣe ẹyẹ ìkẹyìn fún ìyá àgbà*. *Ẹ ṣe* *Ọmọ rere a gbeyin àwa náà bí ti ìyá àgbà Awikonko lójú ọ l'ọ̀rọ̀ , kọ l'ọ̀rọ̀ ó gbọ* July 10, 2018ÌYÁ AGBA OLUDASILE ÌWÉ IROYIN AWIKONKO KÍ AYÉ PÉ OD'IGBA Ó ṢE Yoruba bọ wọ́n ní ẹ kú ìrójú ń gbẹyín ẹ kú ewu ọmọ. Bẹẹ naa ni ìwé mimọ...Read More